Übersetzung der Bedeutungen von dem heiligen Quran - Yorubische Übersetzung * - Übersetzungen

PDF XML CSV Excel API
Please review the Terms and Policies

Übersetzung der Bedeutungen Vers: (66) Surah / Kapitel: Al -I-‘Imrân
هَٰٓأَنتُمۡ هَٰٓؤُلَآءِ حَٰجَجۡتُمۡ فِيمَا لَكُم بِهِۦ عِلۡمٞ فَلِمَ تُحَآجُّونَ فِيمَا لَيۡسَ لَكُم بِهِۦ عِلۡمٞۚ وَٱللَّهُ يَعۡلَمُ وَأَنتُمۡ لَا تَعۡلَمُونَ
Ẹ̀yin ni ìwọ̀nyí tí ẹ̀ ń jiyàn nípa ohun tí ẹ nímọ̀ nípa rẹ̀! Kí ni ó tún ń mu yín jiyàn nípa ohun tí ẹ ò nímọ̀ nípa rẹ̀?¹ Allāhu nímọ̀. Ẹ̀yin kò sì nímọ̀.
1. Ìyẹn ni pé, ’Islām tí Ànábì Mūsā - kí ọlà Allāhu máa bá a - àti ’Islām tí Ànábì ‘Īsā ọmọ Mọryam - kí ọlà Allāhu máa bá a - mú wá, ó ti dojúrú pátápátá mọ́ àwọn ọmọ ’Isrọ̄’īl lọ́wọ́, tòhun ti bí wọ́n ṣe bá àwọn Ànábì méjèèjì lògbà pọ̀. Nítorí náà, kí ni wọ́n fẹ́ wá rí sọ nípa ’Islām tí Ànábì ’Ibrọ̄hīm - kí ọlà Allāhu máa bá a - mú wá, ẹni tí wọn kò bá láyé, bí kò ṣe ìsọkúsọ irú èyí tí wọ́n ń sọ nípa àwọn Ànábì tiwọn, Ànábì Mūsā àti Ànábì ‘Īsā - kí ọlà Allāhu máa bá àwọn méjèèjì -.
Arabische Interpretationen von dem heiligen Quran:
 
Übersetzung der Bedeutungen Vers: (66) Surah / Kapitel: Al -I-‘Imrân
Suren/ Kapiteln Liste Nummer der Seite
 
Übersetzung der Bedeutungen von dem heiligen Quran - Yorubische Übersetzung - Übersetzungen

Übersetzung der Quran-Bedeutung in Yoruba Sprache von Abu Rahima Mikhail Aikweiny in 1432 H.

Schließen