Traducción de los significados del Sagrado Corán - Traducción Yoruba * - Índice de traducciones

PDF XML CSV Excel API
Please review the Terms and Policies

Traducción de significados Versículo: (150) Capítulo: Sura Al-‘Imrán
بَلِ ٱللَّهُ مَوۡلَىٰكُمۡۖ وَهُوَ خَيۡرُ ٱلنَّٰصِرِينَ
Allāhu sì ni Alárànṣe yín.¹ Ó sì lóore jùlọ nínú àwọn alárànṣe.²
1. Ohun tí “bal” (bí kò ṣe pé) ìbẹ̀rẹ̀ āyah yìí kó sínú ni pé, “ẹ má tẹ̀lé àwọn aláìgbàgbọ́ lẹ́yìn ìgbàgbọ́ òdodo yín nítorí pé, wọn kò lè ṣe àrànṣe fún yín bí kò ṣe Allāhu, Òun ni Alárànṣe yín”.
2. Ẹ wo ìtọsẹ̀-ọ̀rọ̀ sūrah as-Sọffāt; 37:125.
Las Exégesis Árabes:
 
Traducción de significados Versículo: (150) Capítulo: Sura Al-‘Imrán
Índice de Capítulos Número de página
 
Traducción de los significados del Sagrado Corán - Traducción Yoruba - Índice de traducciones

Traducción de los significados del Sagrado Corán al idioma Yoruba por Abu Rahima Mikael Aikweiny. Año de impresión: 1432H.

Cerrar