Traducción de los significados del Sagrado Corán - Traducción Yoruba * - Índice de traducciones

PDF XML CSV Excel API
Please review the Terms and Policies

Traducción de significados Versículo: (39) Capítulo: Sura Saad
هَٰذَا عَطَآؤُنَا فَٱمۡنُنۡ أَوۡ أَمۡسِكۡ بِغَيۡرِ حِسَابٖ
Èyí ni ọrẹ Wa. Nítorí náà, fi tọrẹ tàbí kí ó mú un dání¹ láì níí ní ìṣírò.²
1. Gbólóhùn yìí “Èyí ni ọrẹ Wa.” Ó túmọ̀ sí “èyí ni àwọn dúkìá ayé tí A fi ta ọ́ ní ọrẹ”. Ìtúmọ̀ yìí sì ni mo lò. Àmọ́ “Èyí ni ọrẹ Wa.” tún túmọ̀ sí “èyí ni àwọn àlùjànnú tí A fi ta ọ́ ní ọrẹ.” Pẹ̀lú ìtúmọ̀ kejì yìí. Ohun tí ó máa jẹ́ ìtúmọ̀ fún gbólóhùn ìparí āyah náà máa lọ báyìí pé, “Tu àwọn àlùjànnú tí o bá fẹ́ tú kúrò lórí ìgbèkùn sílẹ̀ tàbí kí o de èyí tí ó bá fẹ́ mọ́lẹ̀ sórí ìgbèkùn, kò sì níí sí ìbéèrè fún ọ lórí rẹ̀ ní Ọjọ́ Ìṣírò iṣẹ́.
2. Ìyẹn ni pé, Ànábì Sulaemọ̄n - kí ọlà Allāhu máa bá a - kò níí ṣe ìṣírò ní Ọjọ́ Ìṣírò-iṣẹ́ lórí èyí tí ó ná síta àti èyí tí ó ná fún ìgbádùn ara rẹ̀ nílé ayé.
Las Exégesis Árabes:
 
Traducción de significados Versículo: (39) Capítulo: Sura Saad
Índice de Capítulos Número de página
 
Traducción de los significados del Sagrado Corán - Traducción Yoruba - Índice de traducciones

Traducción de los significados del Sagrado Corán al idioma Yoruba por Abu Rahima Mikael Aikweiny. Año de impresión: 1432H.

Cerrar