Traduzione dei Significati del Sacro Corano - Traduzione in yoruba * - Indice Traduzioni

PDF XML CSV Excel API
Please review the Terms and Policies

Traduzione dei significati Versetto: (14) Sura: An-Nisâ’
وَمَن يَعۡصِ ٱللَّهَ وَرَسُولَهُۥ وَيَتَعَدَّ حُدُودَهُۥ يُدۡخِلۡهُ نَارًا خَٰلِدٗا فِيهَا وَلَهُۥ عَذَابٞ مُّهِينٞ
Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì yapa (àṣẹ) Allāhu àti Òjíṣẹ́ Rẹ̀, tí ó sì ń tayọ àwọn ẹnu-ààlà tí Allāhu gbékalẹ̀, (Allāhu) yóò mú un wọ inú Iná kan. Olùṣegbére ni nínú rẹ̀. Ìyà tí í yẹpẹrẹ ẹ̀dá sì ń bẹ fún un.¹
1. Kíyè sí i, kò bá òfin ’Islām mu láti pín ogún ara ẹni sílẹ̀. Àti pé bí ènìyàn kò bá tí ì kú, dúkìá rẹ̀ kò ì di ogún fún ẹnì kan kan. Bákan náà, kí ẹnikẹ́ni má ṣe lérò pé tí òun bá ti ka àwọn āyah ogún pípín, òun ti nímọ̀ nípa ogún pípín nìyẹn. Rárá o. Ènìyàn gbọ́dọ̀ ka àwọn tírà tí àwọn onímọ̀ ẹ̀sìn ’Islām fi ṣàlàyé nípa ogún pípín. Fómúlà nìkan ni àwọn āyah ogún pípín jẹ́, bí a ṣe máa lo àwọn fọ́múlà náà wà nínú àwọn tírà ogún pípín.
Esegesi in lingua araba:
 
Traduzione dei significati Versetto: (14) Sura: An-Nisâ’
Indice delle Sure Numero di pagina
 
Traduzione dei Significati del Sacro Corano - Traduzione in yoruba - Indice Traduzioni

Traduzione dei significati del Nobile Corano in yoruba, di Shaikh Abu Rahima Mika'il 'Aikweiny, ed. 1432 H.

Chiudi