Bản dịch ý nghĩa nội dung Qur'an - Dịch thuật tiếng Yoruba * - Mục lục các bản dịch

PDF XML CSV Excel API
Please review the Terms and Policies

Ý nghĩa nội dung Câu: (9) Chương: Chương Yunus
إِنَّ ٱلَّذِينَ ءَامَنُواْ وَعَمِلُواْ ٱلصَّٰلِحَٰتِ يَهۡدِيهِمۡ رَبُّهُم بِإِيمَٰنِهِمۡۖ تَجۡرِي مِن تَحۡتِهِمُ ٱلۡأَنۡهَٰرُ فِي جَنَّٰتِ ٱلنَّعِيمِ
Dájúdájú àwọn tó gbàgbọ́ ní òdodo, tí wọ́n sì ṣe àwọn iṣẹ́ rere, Olúwa wọn yóò fi ìgbàgbọ́ òdodo wọn tọ́ wọn sọ́nà.¹ Àwọn odò yó sì máa ṣàn ní ìsàlẹ̀ ọ̀dọ̀ wọn nínú Ọgbà Ìdẹ̀ra.
1. “Ìgbàgbọ́ òdodo” tó jẹyọ nínú gbólóhùn “àwọn tó gbàgbọ́ ní òdodo” àti gbólóhùn “Olúwa wọn yóò fi ìgbàgbọ́ òdodo wọn tọ́ wọn sọ́nà.” jẹ́ n̄ǹkan kan náà. Ìtúmọ̀ rẹ̀ sì ni ìwọ̀nyí:
(Ìkíní); Ìgbàgbọ́ òdodo yóò máa ṣe atọ́nà onígbàgbọ́ òdodo lọ síbi àlékún iṣẹ́ rere títí ọjọ́ ikú rẹ̀.
(Ìkejì); Ìgbàgbọ́ òdodo yóò yọ sí onígbàgbọ́ òdodo ní àwòrán ẹ̀dá tó rẹwà jùlọ pẹ̀lú ìmọ́lẹ̀ tó lágbára jùlọ lọ́jọ́ tí onígbàgbọ́ òdodo náà bá jíǹde nínú sàréè rẹ̀ lọ́jọ́ Àjíǹde. Àwòrán iṣẹ́ rere yìí yó sì máa darí rẹ̀ lọ títí olówó rẹ̀ máa fi wọ inú Ọgbà Ìdẹ̀ra.
Các Tafsir tiếng Ả-rập:
 
Ý nghĩa nội dung Câu: (9) Chương: Chương Yunus
Mục lục các chương Kinh Số trang
 
Bản dịch ý nghĩa nội dung Qur'an - Dịch thuật tiếng Yoruba - Mục lục các bản dịch

Bản dịch ý nghĩa nội dung Kinh Qur'an bằng tiếng Yoruba, dịch thuật bởi Sheikh Abu Rahimah Mika-il Ikweeni, xuất bản năm 1432 A.H

Đóng lại