Übersetzung der Bedeutungen von dem heiligen Quran - Yorubische Übersetzung * - Übersetzungen

PDF XML CSV Excel API
Please review the Terms and Policies

Übersetzung der Bedeutungen Vers: (46) Surah / Kapitel: Al -I-‘Imrân
وَيُكَلِّمُ ٱلنَّاسَ فِي ٱلۡمَهۡدِ وَكَهۡلٗا وَمِنَ ٱلصَّٰلِحِينَ
Ó máa bá àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ lórí ìtẹ́ ní òpóǹló àti nígbà tó bá dàgbà.¹ Ó sì wà nínú àwọn ẹni rere.”
1. Láti ọ̀dọ̀ bàbá Huraerah - kí Allāhu yọ́nú sí i -, láti ọ̀dọ̀ Ànábì - kí ìkẹ́ àti ọlà Allāhu máa bá a -, ó sọ pé, “Kò sí ẹni tí ó sọ̀rọ̀ lórí ìtẹ́ ní òpóǹló àfi ọmọdé mẹ́ta; Ànábì ‘Īsā ọmọ Mọryam - kí ọlà Allāhu máa bá a -, ọmọdé kan ní àsìkò Juraej àti ọmọdé kan mìíràn.” Bukọ̄riy, Muslim àti ’Ahmad, èyí ni ẹ̀gbàwá ’Ahmad.
Arabische Interpretationen von dem heiligen Quran:
 
Übersetzung der Bedeutungen Vers: (46) Surah / Kapitel: Al -I-‘Imrân
Suren/ Kapiteln Liste Nummer der Seite
 
Übersetzung der Bedeutungen von dem heiligen Quran - Yorubische Übersetzung - Übersetzungen

Übersetzung der Quran-Bedeutung in Yoruba Sprache von Abu Rahima Mikhail Aikweiny in 1432 H.

Schließen