Traduzione dei Significati del Sacro Corano - Traduzione in yoruba * - Indice Traduzioni

PDF XML CSV Excel API
Please review the Terms and Policies

Traduzione dei significati Versetto: (46) Sura: Al ‘Imrân
وَيُكَلِّمُ ٱلنَّاسَ فِي ٱلۡمَهۡدِ وَكَهۡلٗا وَمِنَ ٱلصَّٰلِحِينَ
Ó máa bá àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ lórí ìtẹ́ ní òpóǹló àti nígbà tó bá dàgbà.¹ Ó sì wà nínú àwọn ẹni rere.”
1. Láti ọ̀dọ̀ bàbá Huraerah - kí Allāhu yọ́nú sí i -, láti ọ̀dọ̀ Ànábì - kí ìkẹ́ àti ọlà Allāhu máa bá a -, ó sọ pé, “Kò sí ẹni tí ó sọ̀rọ̀ lórí ìtẹ́ ní òpóǹló àfi ọmọdé mẹ́ta; Ànábì ‘Īsā ọmọ Mọryam - kí ọlà Allāhu máa bá a -, ọmọdé kan ní àsìkò Juraej àti ọmọdé kan mìíràn.” Bukọ̄riy, Muslim àti ’Ahmad, èyí ni ẹ̀gbàwá ’Ahmad.
Esegesi in lingua araba:
 
Traduzione dei significati Versetto: (46) Sura: Al ‘Imrân
Indice delle Sure Numero di pagina
 
Traduzione dei Significati del Sacro Corano - Traduzione in yoruba - Indice Traduzioni

Traduzione dei significati del Nobile Corano in yoruba, di Shaikh Abu Rahima Mika'il 'Aikweiny, ed. 1432 H.

Chiudi