Traduction des sens du Noble Coran - Traduction en yorouba * - Lexique des traductions

PDF XML CSV Excel API
Please review the Terms and Policies

Traduction des sens Verset: (46) Sourate: AL ‘IMRÂN
وَيُكَلِّمُ ٱلنَّاسَ فِي ٱلۡمَهۡدِ وَكَهۡلٗا وَمِنَ ٱلصَّٰلِحِينَ
Ó máa bá àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ lórí ìtẹ́ ní òpóǹló àti nígbà tó bá dàgbà.¹ Ó sì wà nínú àwọn ẹni rere.”
1. Láti ọ̀dọ̀ bàbá Huraerah - kí Allāhu yọ́nú sí i -, láti ọ̀dọ̀ Ànábì - kí ìkẹ́ àti ọlà Allāhu máa bá a -, ó sọ pé, “Kò sí ẹni tí ó sọ̀rọ̀ lórí ìtẹ́ ní òpóǹló àfi ọmọdé mẹ́ta; Ànábì ‘Īsā ọmọ Mọryam - kí ọlà Allāhu máa bá a -, ọmọdé kan ní àsìkò Juraej àti ọmọdé kan mìíràn.” Bukọ̄riy, Muslim àti ’Ahmad, èyí ni ẹ̀gbàwá ’Ahmad.
Les exégèses en arabe:
 
Traduction des sens Verset: (46) Sourate: AL ‘IMRÂN
Lexique des sourates Numéro de la page
 
Traduction des sens du Noble Coran - Traduction en yorouba - Lexique des traductions

Traduction des sens du Noble Coran en langue yorouba par Cheikh Abû Rahimah Mikhaïl Aikweiny et publiée en l'an 1432 de l'Hégire.

Fermeture