Traducción de los significados del Sagrado Corán - Traducción Yoruba * - Índice de traducciones

PDF XML CSV Excel API
Please review the Terms and Policies

Traducción de significados Capítulo: Sura Al-Falaq   Versículo:

Suuratul-Falaq

قُلۡ أَعُوذُ بِرَبِّ ٱلۡفَلَقِ
Sọ pé: “Mo sá di Olúwa òwúrọ̀ kùtùkùtù
Las Exégesis Árabes:
مِن شَرِّ مَا خَلَقَ
níbi aburú ohun tí Ó dá,¹
1. Allāhu ni Ẹlẹ́dàá gbogbo n̄ǹkan, ohun rere àti ohun burúkú. Ọ̀kan pàtàkì nínú ohun burúkú nínú àwọn ẹ̀dá tí Allāhu dá ni aṣ-Ṣaetọ̄n àti àwọn ọmọ ogun rẹ̀ bí àjẹ́, oṣó, emèrè, àwọn n̄ǹkan olóró àti àwọn iwọ. Nítorí náà, Èṣù kọ́ ló dá owó àti dúkìá. Ẹni tí ó bá wá tọrọ owó ní ọ̀dọ̀ Èṣù, ó ti di ẹlẹ́bọ, ẹni Èṣù.
Las Exégesis Árabes:
وَمِن شَرِّ غَاسِقٍ إِذَا وَقَبَ
àti níbi aburú òru nígbà tí ó bá ṣóòkùn,
Las Exégesis Árabes:
وَمِن شَرِّ ٱلنَّفَّٰثَٰتِ فِي ٱلۡعُقَدِ
àti níbi aburú àwọn (òpìdán) tó ń fẹnu fátẹ́gùn túẹ́túẹ́ sínú àwọn ońdè,
Las Exégesis Árabes:
وَمِن شَرِّ حَاسِدٍ إِذَا حَسَدَ
àti níbi aburú onílara nígbà tí ó bá ṣe ìlara.”
Las Exégesis Árabes:
 
Traducción de significados Capítulo: Sura Al-Falaq
Índice de Capítulos Número de página
 
Traducción de los significados del Sagrado Corán - Traducción Yoruba - Índice de traducciones

Traducción de los significados del Sagrado Corán al idioma Yoruba por Abu Rahima Mikael Aikweiny. Año de impresión: 1432H.

Cerrar