Check out the new design

Traducción de los significados del Sagrado Corán - Traducción Yoruba - Abu Rahima Mikael * - Índice de traducciones

PDF XML CSV Excel API
Please review the Terms and Policies

Traducción de significados Capítulo: Al-Nass   Versículo:

An-Naas

قُلۡ أَعُوذُ بِرَبِّ ٱلنَّاسِ
Sọ pé: “Mo sá di Olúwa àwọn ènìyàn,
Las Exégesis Árabes:
مَلِكِ ٱلنَّاسِ
Ọba àwọn ènìyàn,
Las Exégesis Árabes:
إِلَٰهِ ٱلنَّاسِ
Ọlọ́hun àwọn ènìyàn,[1]
1. Ìtúmọ̀ “Ọlọ́hun àwọn ènìyàn” ni pé, Ẹni tí àwọn ènìyàn gbọ́dọ̀ máa jọ́sìn fún ní ọ̀nà òdodo, tí wọn kò sì gbọ́dọ̀ jọ́sìn fún ẹlòmíìràn lẹ́yìn Rẹ̀.
Las Exégesis Árabes:
مِن شَرِّ ٱلۡوَسۡوَاسِ ٱلۡخَنَّاسِ
níbi aburú (aṣ-Ṣaetọ̄n) oníròyíròyí, olùsásẹ́yìn (fún ẹni tó bá ń dárúkọ Allāhu[1]).
1. Ọ̀kan pàtàkì nínú àǹfààní àti oore tí ó wà nínú ath-thikār ṣíṣe ni pé, aṣ-Ṣaetọ̄n àti àwọn ọmọ ogun rẹ̀ yóò máa sá sẹ́yìn fún ẹni tí ó bá ń ṣe ath-thikār ní gbogbo ìgbà.
Las Exégesis Árabes:
ٱلَّذِي يُوَسۡوِسُ فِي صُدُورِ ٱلنَّاسِ
(aṣ-Ṣaetọ̄n ni) ẹni tí ó ń kó ròyíròyí sínú àwọn ọkàn ènìyàn.
Las Exégesis Árabes:
مِنَ ٱلۡجِنَّةِ وَٱلنَّاسِ
(Ṣaetọ̄n náà) wà nínú àwọn àlùjànnú àti àwọn ènìyàn.”
Las Exégesis Árabes:
 
Traducción de significados Capítulo: Al-Nass
Índice de Capítulos Número de página
 
Traducción de los significados del Sagrado Corán - Traducción Yoruba - Abu Rahima Mikael - Índice de traducciones

Traducida por Sheij Abu Rahima Michael Aikueyeni.

Cerrar